Orin Dafidi 32:6 BIBELI MIMỌ (BM)

Nítorí náà, kí gbogbo olódodo máa gbadura sí ọ;ní àkókò tí ìpọ́njú bá ń yí lura wọn bí ìṣàn omi ńlá,kò ní dé ọ̀dọ̀ wọn.

Orin Dafidi 32

Orin Dafidi 32:1-11