Orin Dafidi 137:3 BIBELI MIMỌ (BM)

nítorí pé níbẹ̀ ni àwọn tí ó kó wa ní ìgbèkùnti ní kí á kọrin fún àwọn.Àwọn tí ó ń pọ́n wa lójú sọ pé kí á dá àwọn lárayá, wọ́n ní,“Ẹ kọ orin Sioni kan fún wa.”

Orin Dafidi 137

Orin Dafidi 137:1-9