Nọmba 34:19-24 BIBELI MIMỌ (BM)

19. Àwọn olórí náà nìwọ̀nyí: láti inú ẹ̀yà Juda, a yan Kalebu ọmọ Jefune.

20. Láti inú ẹ̀yà Simeoni, a yan Ṣemueli ọmọ Amihudu.

21. Láti inú ẹ̀yà Bẹnjamini, a yan Elidadi ọmọ Kisiloni.

22. Láti inú ẹ̀yà Dani, a yan Buki ọmọ Jogili.

23. Láti inú ẹ̀yà Manase, a yan Hanieli ọmọ Efodu.

24. Láti inú ẹ̀yà Efuraimu, a yan Kemueli ọmọ Ṣifitani.

Nọmba 34