Nọmba 32:21 BIBELI MIMỌ (BM)

tí àwọn ọmọ ogun yín sì ṣetán láti ré odò Jọdani kọjá ní àṣẹ OLUWA láti gbógun ti àwọn ọ̀tá wa títí OLUWA yóo fi pa wọ́n run,

Nọmba 32

Nọmba 32:15-27