Nọmba 26:65 BIBELI MIMỌ (BM)

Nítorí pé OLUWA ti sọ pé gbogbo àwọn ti ìgbà náà ni yóo kú ninu aṣálẹ̀. Kalebu ọmọ Jefune ati Joṣua ọmọ Nuni nìkan ni ó kù lára wọn.

Nọmba 26

Nọmba 26:57-65