Nọmba 23:11 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà náà ni Balaki sọ fún Balaamu pé, “Kí ni ò ń ṣe sí mi yìí? Mo mú ọ wá láti ṣépè lé àwọn ọ̀tá mi, ṣugbọn ò ń súre fún wọn.”

Nọmba 23

Nọmba 23:8-13