Nọmba 21:6 BIBELI MIMỌ (BM)

OLUWA bá rán ọpọlọpọ ejò amúbíiná sí àwọn eniyan náà, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí bù wọ́n jẹ, ọpọlọpọ ninu wọn sì kú.

Nọmba 21

Nọmba 21:1-13