Kronika Kinni 6:20-30 BIBELI MIMỌ (BM)

20. Àwọn tí wọ́n ṣẹ̀ láti ọ̀dọ̀ Geriṣoni nìwọ̀nyí: Libini ni baba Jahati, Jahati bí Sima,

21. Sima bí Joa, Joa bí Ido, Ido bí Sera, Sera sì bí, Jeaterai.

22. Àwọn tí ó ṣẹ̀ láti ọ̀dọ̀ Kohati nìwọ̀nyí: Aminadabu ni baba Kora, Kora ló bí Asiri;

23. Asiri bí Elikana, Elikana bí Ebiasafu, Ebiasafu sì bí Asiri.

24. Asiri ni baba Tahati, Tahati ló bí Urieli, Urieli bí Usaya, Usaya sì bí Saulu.

25. Ọmọ meji ni Elikana bí: Amasai ati Ahimotu.

26. Àwọn ọmọ Ahimotu nìwọ̀nyí: Elikana ni baba Sofai, Sofai ni ó bí Nahati;

27. Nahati bí Eliabu, Eliabu bí Jerohamu, Jerohamu sì bí Elikana.

28. Samuẹli bí ọmọkunrin meji: Joẹli ni àkọ́bí, Abija sì ni ikeji.

29. Àwọn ọmọ Merari nìwọ̀nyí: Mahili ni baba Libini, Libini bí Ṣimei,

30. Ṣimei bí Usali, Usali bí Ṣimea, Ṣimea bí Hagaya, Hagaya sì bí Asaya.

Kronika Kinni 6