Kronika Kinni 22:10 BIBELI MIMỌ (BM)

Ó ní ọmọ náà ni yóo kọ́ ilé fún òun. Yóo jẹ́ ọmọ òun, òun náà yóo sì jẹ́ baba rẹ̀. Ó ní òun óo fìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀ ní Israẹli títí lae.

Kronika Kinni 22

Kronika Kinni 22:4-19