Kronika Kinni 19:4 BIBELI MIMỌ (BM)

Nítorí náà, Hanuni mú àwọn oníṣẹ́ Dafidi, ó fá irùngbọ̀n wọn, ó gé ẹ̀wù wọn ní ìbàdí, ó sì lé wọn jáde.

Kronika Kinni 19

Kronika Kinni 19:1-11