Kronika Kinni 19:10 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà tí Joabu rí i pé àwọn ọ̀tá ti gbógun ti òun níwájú ati lẹ́yìn, ó yan àwọn akọni ninu àwọn ọmọ ogun Israẹli láti dojú kọ àwọn ará Siria.

Kronika Kinni 19

Kronika Kinni 19:5-11