25. Eberi, Pelegi, Reu;
26. Serugi, Nahori, Tẹra;
27. Abramu, tí a tún ń pè ní Abrahamu.
28. Àwọn ọmọ Abrahamu ni Isaaki ati Iṣimaeli.
29. Àkọsílẹ̀ ìran wọn nìyí: Nebaiotu ni àkọ́bí Iṣimaeli, lẹ́yìn náà ni ó bí Kedari, Adibeeli, ati Mibisamu;
30. Miṣima, Duma ati Masa; Hadadi ati Tema;