Kronika Kinni 1:25-30 BIBELI MIMỌ (BM)

25. Eberi, Pelegi, Reu;

26. Serugi, Nahori, Tẹra;

27. Abramu, tí a tún ń pè ní Abrahamu.

28. Àwọn ọmọ Abrahamu ni Isaaki ati Iṣimaeli.

29. Àkọsílẹ̀ ìran wọn nìyí: Nebaiotu ni àkọ́bí Iṣimaeli, lẹ́yìn náà ni ó bí Kedari, Adibeeli, ati Mibisamu;

30. Miṣima, Duma ati Masa; Hadadi ati Tema;

Kronika Kinni 1