Kronika Keji 16:13-14 BIBELI MIMỌ (BM)

13. Asa kú ní ọdún kọkanlelogoji ìjọba rẹ̀.

14. Wọ́n sin ín sinu ibojì òkúta tí ó gbẹ́ fúnrarẹ̀ ní ìlú Dafidi. Wọ́n tẹ́ ẹ sórí àkéte, tí ó kún fún oniruuru turari tí àwọn tí wọ́n ń ṣe turari ṣe. Wọ́n sì dá iná ńlá kan láti ṣọ̀fọ̀ rẹ̀.

Kronika Keji 16