Jobu 19:11-13 BIBELI MIMỌ (BM) Ibinu rẹ̀ ń jó mi bí iná,ó kà mí kún ọ̀tá rẹ̀. Àwọn ọmọ ogun rẹ̀ kó ara wọn jọ,wọ́n dó tì