Jobu 16:11-14 BIBELI MIMỌ (BM)

11. Ọlọrun fà mí lé eniyan burúkú lọ́wọ́,ó mú kí n ṣubú sí ọwọ́ àwọn ìkà.

12. Nígbà tí ó dára fún mi,ó fi ẹ̀yìn mi wọ́nlẹ̀,ó fún mi lọ́rùn, ó gbé mi ṣánlẹ̀,ó sì gbọ̀n mí yẹ́bẹ́yẹ́bẹ́;ó yàn mí sọjú bí àmì ìtafà sí.

13. Àwọn tafàtafà rẹ̀ yí mi ká,ó la kíndìnrín mi láìṣàánú mi,ó sì tú òróòro mi jáde.

14. Ó ń gbógun tì mí nígbà gbogbo,ó pakuuru sí mi bí ọmọ ogun.

Jobu 16