Jeremaya 51:41 BIBELI MIMỌ (BM)

OLUWA ní,“Ẹ wò ó bí ogun ti kó Babiloni,Babiloni tí gbogbo ayé ń pọ́nlé!Ó wá di àríbẹ̀rù láàrin àwọn orílẹ̀-èdè!

Jeremaya 51

Jeremaya 51:34-44