Jẹnẹsisi 3:23 BIBELI MIMỌ (BM)

Nítorí náà OLUWA Ọlọrun lé e jáde kúrò ninu ọgbà Edẹni, kí ó lọ máa ro ilẹ̀, ninu èyí tí Ọlọrun ti mú un jáde.

Jẹnẹsisi 3

Jẹnẹsisi 3:22-24