Jẹnẹsisi 18:26 BIBELI MIMỌ (BM)

OLUWA dáhùn, ó ní, “Bí mo bá rí aadọta olódodo ninu ìlú Sodomu, n óo dá gbogbo ìlú náà sí nítorí tiwọn.”

Jẹnẹsisi 18

Jẹnẹsisi 18:24-31