Ìṣe Àwọn Aposteli 7:17 BIBELI MIMỌ (BM)

“Nígbà tí ó fẹ́rẹ̀ tó àkókò tí ìlérí tí Ọlọrun ṣe fún Abrahamu yóo ṣẹ, àwọn eniyan náà wá túbọ̀ ń pọ̀ níye ní Ijipti.

Ìṣe Àwọn Aposteli 7

Ìṣe Àwọn Aposteli 7:13-27