Ìṣe Àwọn Aposteli 22:26 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà tí balogun ọ̀rún gbọ́, ó lọ sọ́dọ̀ ọ̀gágun, ó bi í pé, “Kí lẹ fẹ́ ṣe? Ọmọ ìbílẹ̀ Romu ni ọkunrin yìí o!”

Ìṣe Àwọn Aposteli 22

Ìṣe Àwọn Aposteli 22:22-30