Ìṣe Àwọn Aposteli 22:18 BIBELI MIMỌ (BM)

Mo rí Oluwa tí ó ń sọ fún mi pé, ‘Jáde kúrò ní Jerusalẹmu kíákíá, nítorí wọn kò ní gba ẹ̀rí tí ò ń jẹ́ nípa mi.’

Ìṣe Àwọn Aposteli 22

Ìṣe Àwọn Aposteli 22:9-28