Ẹkisodu 9:18 BIBELI MIMỌ (BM)

OLUWA ní, “Wò ó, níwòyí ọ̀la, n óo da yìnyín bo ilẹ̀, irú èyí tí kò sí ní ilẹ̀ Ijipti rí, láti ọjọ́ tí wọ́n ti tẹ̀ ẹ́ dó títí di òní yìí.

Ẹkisodu 9

Ẹkisodu 9:16-25