Diutaronomi 21:10 BIBELI MIMỌ (BM)

“Nígbà tí ẹ bá lọ bá àwọn ọ̀tá yín jagun, tí OLUWA Ọlọrun yín bá fi wọ́n le yín lọ́wọ́, tí ẹ bá sì kó wọn lẹ́rú;

Diutaronomi 21

Diutaronomi 21:1-16