Daniẹli 2:12 BIBELI MIMỌ (BM)

Nítorí náà inú ọba ru, ó sì bínú gidigidi, ó bá pàṣẹ pé kí wọ́n pa gbogbo àwọn ọlọ́gbọ́n Babiloni run.

Daniẹli 2

Daniẹli 2:5-14