Daniẹli 11:10 BIBELI MIMỌ (BM)

“Àwọn ọmọ ọba Siria yóo gbá ogun ńlá jọ, wọn yóo sì kó ogun wọn wá, wọn yóo jà títí wọn yóo fi wọ ìlú olódi ti ọ̀tá wọn.

Daniẹli 11

Daniẹli 11:6-15