Àwọn Ọba Keji 9:26 BIBELI MIMỌ (BM)

pé, ‘Mo rí i bí o ti pa Naboti ati àwọn ọmọ rẹ̀ lánàá, dájúdájú n óo jẹ ọ́ níyà ninu oko kan náà.’ Nítorí náà gbé òkú rẹ̀ jù sinu oko Naboti gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ OLUWA.”

Àwọn Ọba Keji 9

Àwọn Ọba Keji 9:23-32