Àwọn Ọba Keji 17:25 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà tí wọ́n kọ́kọ́ dé ibẹ̀, wọn kò bẹ̀rù OLUWA, nítorí náà OLUWA rán àwọn kinniun sí ààrin wọn, wọ́n sì pa ninu àwọn eniyan tí ọba Asiria kó wá.

Àwọn Ọba Keji 17

Àwọn Ọba Keji 17:23-29