Àwọn Adájọ́ 9:25 BIBELI MIMỌ (BM)

Àwọn ará ìlú Ṣekemu bá rán àwọn kan ninu wọn, wọ́n lọ ba ní ibùba ní orí òkè de Abimeleki. Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí dá gbogbo àwọn tí wọn ń kọjá lọ́nà; ni ìròyìn bá kan Abimeleki.

Àwọn Adájọ́ 9

Àwọn Adájọ́ 9:20-31