Àwọn Adájọ́ 7:9 BIBELI MIMỌ (BM)

OLUWA sọ fún un ní òru ọjọ́ kan náà pé, “Gbéra, lọ gbógun ti àgọ́ náà, nítorí pé mo ti fi lé ọ lọ́wọ́.

Àwọn Adájọ́ 7

Àwọn Adájọ́ 7:1-19