Àwọn Adájọ́ 6:2 BIBELI MIMỌ (BM)

Àwọn ará Midiani lágbára ju àwọn ọmọ Israẹli lọ tóbẹ́ẹ̀ tí àwọn ọmọ Israẹli fi ṣe ibi tí wọn ń sápamọ́ sí lórí àwọn òkè, ninu ihò àpáta, ati ibi ààbò mìíràn ninu òkè.

Àwọn Adájọ́ 6

Àwọn Adájọ́ 6:1-6