Àwọn Adájọ́ 17:6 BIBELI MIMỌ (BM)

Kò sí ọba ní ilẹ̀ Israẹli ní gbogbo àkókò náà, nítorí náà ohun tí ó bá tọ́ lójú olukuluku ni olukuluku ń ṣe.

Àwọn Adájọ́ 17

Àwọn Adájọ́ 17:2-7