Àwọn Adájọ́ 16:23 BIBELI MIMỌ (BM)

Ní ọjọ́ kan, àwọn ọba Filistini kó ara wọn jọ láti rú ẹbọ ńlá kan sí Dagoni, oriṣa wọn, ati láti ṣe àríyá pé oriṣa wọn ni ó fi Samsoni ọ̀tá wọn lé wọn lọ́wọ́.

Àwọn Adájọ́ 16

Àwọn Adájọ́ 16:14-31