Àwọn Adájọ́ 13:24 BIBELI MIMỌ (BM)

Nígbà tí ó yá, obinrin náà bí ọmọkunrin kan, ó sì sọ ọ́ ní Samsoni. Ọmọ náà bẹ̀rẹ̀ sí dàgbà, OLUWA sì bukun un.

Àwọn Adájọ́ 13

Àwọn Adájọ́ 13:15-25