Àwọn Adájọ́ 11:38 BIBELI MIMỌ (BM)

Baba rẹ̀ bá ní kí ó máa lọ fún oṣù meji. Òun ati àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ bá lọ sí orí òkè, wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí sọkún, nítorí pé ó níláti kú, láì mọ ọkunrin.

Àwọn Adájọ́ 11

Àwọn Adájọ́ 11:33-39