Sáàmù 98:3-6 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

3. Ó rántí ìfẹ́ Rẹ̀ àti òtítọ́ Rẹ̀ fún àwọn ará ilé Ísírẹ́lì;gbogbo òpin ayé ni ó ti ríiṣẹ́ ìgbàlà Ọlọ́run wa.

4. Ẹ hó ìhó ayọ̀ sí Olúwa, gbogbo ayé,ẹ bu sáyọ̀, ẹ kọrin ìyìn

5. Ẹ fi dùùrù kọrin sí Olúwa, pẹ̀lú dùùrù àti ìró ohùn orin mímọ́,

6. Pẹ̀lú ìpè àti fèrèẹ hó fún ayọ̀ níwájú Olúwa Ọba.

Sáàmù 98