Sáàmù 73:26-28 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

26. Ara mi àti ọkàn mi leè kùnàṣùgbọ́n Ọlọ́run ni agbára ẹ̀mí miàti ìpín mi títí láé.

27. Àwọn tí ó jìnnà sí ọ yóò ṣègbéìwọ ti pa gbogbo wọn run;tí ń ṣe àgbèrè kiri kúrò lọ́dọ̀ Rẹ

28. Ṣùgbọ́n ní ti èmi, ó dára láti súnmọ́ Ọlọ́runÈmi ti fi Olúwa Ọlọ́run ṣe ààbò mi;Kí èmi ó lè máa sọ̀rọ̀ iṣẹ́ Rẹ.

Sáàmù 73