Sáàmù 47:1-4 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

1. Ẹ pàtẹ́wọ́, gbogbo ẹ̀yin ènìyànẹ hó sí Ọlọ́run pẹ̀lú orin ayọ̀ tó rinlẹ̀

2. Báwo ni Olúwa ọ̀gá ògo ti ni ẹ̀rù tóọba ńlá lórí gbogbo ayé

3. Ó ṣẹ́ àwọn orílẹ̀ èdè lábẹ́ waàwọn ènìyàn lábẹ́ ẹsẹ̀ wa

4. Ó mú ilẹ̀ ìní wa fún waọlá Jákọ́bù, ẹni tí ó fẹ́ wa

Sáàmù 47