Sáàmù 31:4-6 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

4. Yọ mí jáde kúrò nínú àwọ̀n tí wọ́n dẹ pamọ́ fún mi,nítorí ìwọ ni ìsádi mi.

5. Ní ọwọ́ Rẹ ni mo fi ẹ̀mí mi lé;ìwọ ni ó tí rà mí padà, Olúwa, Ọlọ́run òtítọ́.

6. Èmi ti kórìíra àwọn ẹni tí ń fi yè sí òrìṣà tí kò níye lórí;ṣùgbọ́n èmi gbẹ́kẹ̀lé Olúwa.

Sáàmù 31