Sáàmù 141:5-8 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

5. Jẹ́ kí olódodo lù mí: ìṣeun ni ó jẹ́:jẹ́ kí ó bá mi wí, ó jẹ́ òróró ní orí mi.Tí kì yóò fọ́ mí ní orí.Ṣíbẹ̀ àdúrà mi wá láí sí ìṣe àwọn olùṣe búburú

6. A ó ju àwọn alákòóso sílẹ̀ láti bẹ̀bẹ̀ òkúta,àwọn ẹni búburú yóò kọ pé àwọn ọ̀rọ̀ mi dùn.

7. Egungun wa tàn kálẹ̀ ni ẹnuisà òkú, Bí ẹni tí ó ń tilẹ̀ tí ó sì ń la ilẹ̀,

8. Ṣùgbọ́n ojú mi wá ẹ, Olúwa, Ọlọ́run;nínú Rẹ̀ ni èmi ti rí ààbò, má ṣe mú mi fún ikú.

Sáàmù 141