Sáàmù 120:6-7 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

6. Ó ti pẹ́ tí èmi ti ń gbéláàrin àwọn tí ó kóríra àlàáfíà.

7. Ènìyàn àlàáfíà ni mí;ṣùgbọ́n nígbà tí mo bá sọ̀rọ̀, ogun ni ti wọn.

Sáàmù 120