Sáàmù 106:1-4 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

1. Yin Olúwa Ẹ fi ìyìn fún Olúwa, nítorí tí o ṣeun.Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí tí ó ṣeun;Nítorí tí ìfẹ́ Rẹ̀ dúró láéláé.

2. Ta ni ó le ròyìn iṣẹ́ agbára Olúwata ni lè sọ nípa ìyìn Rẹ̀?

3. Ìbùkún ni fún àwọn tí ń pa ìdájọ́ mọ́?Ẹni tí tí ń ṣe ohun tí ó tọ́

4. Rántí mi, Olúwa,Nígbà tí ó bá fi ojú rere Rẹ̀ hàn,wá sí ìhà mi nígbà tí ìwọ bá gbà wọ́n,

Sáàmù 106