Róòmù 9:8 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Èyí nì ni pé, kì í ṣe àwọn ọmọ nípa ti ara, ni ọmọ Ọlọ́run: ṣùgbọ́n àwọn ọmọ ìlérí ni a kà ní irú ọmọ.

Róòmù 9

Róòmù 9:1-15