Onídájọ́ 8:32 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Gídíónì ọmọ Jóásì kú ní ògbólógbó ọjọ́ rẹ̀, ó sì pọ̀ ní ọjọ́ orí, wọ́n sì sin-ín sí ibojì baba rẹ̀ ní Ófírà ti àwọn ará Ábíésérì.

Onídájọ́ 8

Onídájọ́ 8:29-35