Onídájọ́ 7:9 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ní òru ọjọ́ náà Olúwa sọ fún Gídíónì pé, “Dìde, dojú ogun kọ ibùdó ogun àwọn ará Mídíánì nítorí èmi yóò fi lé ọ lọ́wọ́.

Onídájọ́ 7

Onídájọ́ 7:3-13