Onídájọ́ 6:27 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Gídíónì mú mẹ́wàá nínú àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, ó sì ṣe bí Olúwa ti pàṣẹ fún un ṣùgbọ́n, nítorí ó bẹ̀rù àwọn ará ilé bàbá rẹ̀ àti àwọn ènìyàn ìlú náà kò ṣe é ní ọ̀sán, òru ni ó ṣe.

Onídájọ́ 6

Onídájọ́ 6:24-30