Onídájọ́ 20:4 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Ará Léfì náà, ọkọ obìrin tí wọ́n pa fèsì pé, “Èmi àti àlè mi wá sí Gíbíà ti àwọn ará Bẹ́ńjámínì láti sùn di ilẹ̀ mọ́ níbẹ̀.

Onídájọ́ 20

Onídájọ́ 20:1-7