Onídájọ́ 11:33 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Òun sì ṣẹ́gun wọn, ó sì pa wọ́n ní àpa tán láti Áróérì títí dé agbègbè Mínítì, ó jẹ́ ogún ìlú, títí dé Abeli-Kérámímù. Báyìí ni Ísírẹ́lì ti ṣẹ́gun àwọn ará Ámónì.

Onídájọ́ 11

Onídájọ́ 11:32-34