Nọ́ḿbà 9:23 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nípa àṣẹ Olúwa ni wọ́n ń pa ibùdó wọn, nípa àṣẹ Olúwa náà sì ni wọ́n ń gbéra. Wọ́n gbọ́ràn sí àṣẹ Olúwa ní ìbámu pẹ̀lú àṣẹ Olúwa láti ẹnu Mósè.

Nọ́ḿbà 9

Nọ́ḿbà 9:22-23