Nọ́ḿbà 4:28 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Èyí ni iṣẹ́ ìdílé àwọn Gáṣónì ni Àgọ́ Ìpàdé Ítamárì, ọmọ Árónì tí í ṣe àlùfáà ni yóò sì jẹ alábojútó iṣẹ́ wọn.

Nọ́ḿbà 4

Nọ́ḿbà 4:25-36