Nọ́ḿbà 34:2 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

“Pàṣẹ fún àwọn ọmọ Ísírẹ́lì, kí o sì sọ fún wọn pé: ‘Tí ẹ bá wọ Kénánì, ilẹ̀ tí a ó fi fún yín, gẹ́gẹ́ bí ogún yín yóò ní ààlà wọn yí:

Nọ́ḿbà 34

Nọ́ḿbà 34:1-7